BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Fayemi: Àwọn àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè níbi ìbúra
16 Ọ̀wàrà 2018
Awọn awọran to joju ni gbese nibi ayẹyẹ iburawọle sipo Fayemi ni Ado Ekiti
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n duro ki ayẹyẹ naa bẹrẹ
Àkọlé àwòrán,
Awọn lọbalọba ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa
Àkọlé àwòrán,
Oni nkan laa jẹ o ṣẹ e .Fayemi balẹ biba sibi ayẹyẹ iburawole
Àkọlé àwòrán,
Awọn Imamuu wa nibẹ lati fi adura ran ijọba tuntun yi lọwọ
Àkọlé àwòrán,
Ko si ayẹyẹ iburawọle ti ko ba si adajọ ti yoo bura fun Gomina tuntun
Àkọlé àwòrán,
Ogbeni Kayode Fayemi ati iyawo rẹ ni wọn jijọ kọwọrin wa ibi ayẹyẹ naa
Àkọlé àwòrán,
Ki lẹ lero wi pẹ alagba Bisi Akande n sọ fun alaga ẹgbẹ APC teleri alagba John Odigie-Oyegun?
Àkọlé àwòrán,
Gbajugbaja osere Odunlade Adekola naa peju sibi ayẹyẹ naa
Àkọlé àwòrán,
Igbakeji Gomina Otunba Bisi Egbeyemi ati Iyawo rẹ n yọ sẹṣẹ
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Eko Akinwumi Ambode naa yọju
Àkọlé àwòrán,
Babajide Sanwoolu naa wa ba Kayode Fayemi yọ
Móríwú
01:03
Fídíò,
Àwọn ọ̀dọ̀ ilẹ̀ Africa ni ìlera ọpọlọ wọn pé jù lọ láàgbáyé-Ìwádìí
, Duration 1,03
04:54
Fídíò,
Agboolé Akọni: Ohun tó fa ìjà láàárín Afonja àti Aláàfin Aole àti bí Alimi ṣe dìtẹ̀gbàjọba lọ́wọ́ Afonja nítorí ẹ̀sìn
, Duration 4,54
01:27
Fídíò,
Ohun tó máa ń mú kí ọkùnrin máa rí àpẹrẹ pé òun lóyún nígbà tí ìyàwó rẹ̀ bá lóyún; COUVAD sydrome ni, ohun tó sì ń fàá rèé
, Duration 1,27
04:16
Fídíò,
Torí pé àwọn èèyàn ò rí ààrín èmi àti Allwell Ademola ni wọ́n fi ń sọ pé a ń fẹ́ra, àmọ́ Ọlọ́run yan án sínú ayé mi láti tọ́ mi sọ́nà – Rotimi Salami oṣere
, Duration 4,16
00:59
Fídíò,
Àwọn awakọ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tò ra epo pẹ̀lú bí owó epo ṣe ń lọ sókè
, Duration 0,59
03:03
Fídíò,
Wo tọkọtaya tó ń gba àwẹ̀ Lent àti Ramadan papọ̀
, Duration 3,03
01:44
Fídíò,
Wo àkóbá tó wà nínú àgbàdo, ẹ̀wà àti ata tí a lọ̀ ní ẹ̀rọ ìlọta fún ẹ̀dọ̀ àti kíndìnrín rẹ
, Duration 1,44
05:52
Fídíò,
Ohun táwọn oníṣẹ̀ṣe sọ fún àjọ INEC lórí ìdìbò àti pàtàkì ọdún Ọ̀ṣun Osogbo tí wọ́n fi yí ọjọ́ ìdìbò gómìnà padà
, Duration 5,52
01:01
Fídíò,
Bí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Iran kan ṣe ń dunnú, làwọn míràn ń kẹ́dún lórí ikú Ayatollah Ali Khamenei olórí Iran
, Duration 1,01
01:20
Fídíò,
Fes el Bali, ìlú 'Mẹ́dínà kékéré' tí ẹ̀sìn àti àṣà ìṣẹ̀mbáyé ti pàdé ara wọn
, Duration 1,20
04:01
Fídíò,
Omi Arinta, omi ńlá tó máa ń yọ̀ nígbàkúgbà tó bá rí ènìyàn ní àyíká rẹ̀
, Duration 4,01
02:42
Fídíò,
Bí nǹkan oṣù rẹ̀ bá ń gba èékánná, ìdodo, àtẹ́lẹwọ́ àtàwọn ẹ̀yà ara tó yàtọ̀ sí ojú ara jáde, ọ̀nà àbáyọ rèé
, Duration 2,42
Trending Now