BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ọṣun State: Gboyega Oyetọla di Gómìnà Ọṣun
27 Bélú 2018
Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2018
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀lúmọ̀ọ́ka ló péjú pésẹ̀ síbi ètò ìbúra wọlé fún Gómìnà Gboyega Oyetọla.
Àkọlé àwòrán,
Alhaji Gboyega Oyetọla n lọ bura gẹgẹ bii gomina tuntun ipinlẹ Ọsun.
Àkọlé àwòrán,
Lara awọn eeyan pataki ti o tun darapọ mọ ipejọpọ naa ni Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Enitan Ogunwusi.
Àkọlé àwòrán,
Adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu
Àkọlé àwòrán,
Gomina Ganduje ti ipinlẹ Kano nibi ibura wọle Gomina Gboyega Oyetọla
Àkọlé àwòrán,
Gomina Gboyega Oyetọla n tọwọ bọwe
Àkọlé àwòrán,
Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo náà kò gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambode
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Ọyọ lewaju, ti Ekiti tẹle e, Gomina Eko si n wo wọn lọọkan
Àkọlé àwòrán,
Gbajugbaja osere Yoruba Fadeyi Oloro niyii lẹgbẹ Ataoja ti Osogbo, Oba Jimoh Olanipekun pẹlu iyawo rẹ
Àkọlé àwòrán,
Gboyega Oyetọla bura wọle gẹgẹ bii gomina tuntun ipinlẹ Ọsun.
Àkọlé àwòrán,
Gbajugbaja osere Yoruba Fadeyi Oloro
Àkọlé àwòrán,
Awọn eniyan ipinlẹ Ọṣun sọ ohun ti wọn n reti lọwọ gomina tuntun
Àkọlé àwòrán,
Ara ipinlẹ̀ Ọṣun
Móríwú
01:03
Fídíò,
Àwọn ọ̀dọ̀ ilẹ̀ Africa ni ìlera ọpọlọ wọn pé jù lọ láàgbáyé-Ìwádìí
, Duration 1,03
04:54
Fídíò,
Agboolé Akọni: Ohun tó fa ìjà láàárín Afonja àti Aláàfin Aole àti bí Alimi ṣe dìtẹ̀gbàjọba lọ́wọ́ Afonja nítorí ẹ̀sìn
, Duration 4,54
01:27
Fídíò,
Ohun tó máa ń mú kí ọkùnrin máa rí àpẹrẹ pé òun lóyún nígbà tí ìyàwó rẹ̀ bá lóyún; COUVAD sydrome ni, ohun tó sì ń fàá rèé
, Duration 1,27
04:16
Fídíò,
Torí pé àwọn èèyàn ò rí ààrín èmi àti Allwell Ademola ni wọ́n fi ń sọ pé a ń fẹ́ra, àmọ́ Ọlọ́run yan án sínú ayé mi láti tọ́ mi sọ́nà – Rotimi Salami oṣere
, Duration 4,16
00:59
Fídíò,
Àwọn awakọ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tò ra epo pẹ̀lú bí owó epo ṣe ń lọ sókè
, Duration 0,59
03:03
Fídíò,
Wo tọkọtaya tó ń gba àwẹ̀ Lent àti Ramadan papọ̀
, Duration 3,03
01:44
Fídíò,
Wo àkóbá tó wà nínú àgbàdo, ẹ̀wà àti ata tí a lọ̀ ní ẹ̀rọ ìlọta fún ẹ̀dọ̀ àti kíndìnrín rẹ
, Duration 1,44
05:52
Fídíò,
Ohun táwọn oníṣẹ̀ṣe sọ fún àjọ INEC lórí ìdìbò àti pàtàkì ọdún Ọ̀ṣun Osogbo tí wọ́n fi yí ọjọ́ ìdìbò gómìnà padà
, Duration 5,52
01:01
Fídíò,
Bí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Iran kan ṣe ń dunnú, làwọn míràn ń kẹ́dún lórí ikú Ayatollah Ali Khamenei olórí Iran
, Duration 1,01
01:20
Fídíò,
Fes el Bali, ìlú 'Mẹ́dínà kékéré' tí ẹ̀sìn àti àṣà ìṣẹ̀mbáyé ti pàdé ara wọn
, Duration 1,20
04:01
Fídíò,
Omi Arinta, omi ńlá tó máa ń yọ̀ nígbàkúgbà tó bá rí ènìyàn ní àyíká rẹ̀
, Duration 4,01
02:42
Fídíò,
Bí nǹkan oṣù rẹ̀ bá ń gba èékánná, ìdodo, àtẹ́lẹwọ́ àtàwọn ẹ̀yà ara tó yàtọ̀ sí ojú ara jáde, ọ̀nà àbáyọ rèé
, Duration 2,42
Trending Now