BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ọdún iléyá 2018: Àwòrán tó jẹ arimaleelọ ni Yidi
21 Ògún 2018
Òní ní ọdún Eid il Adha eleyi tí ọpọ èèyàn mọ sí ọdún iléyá.
Àkọlé àwòrán,
Jakejado agbàyè ni awọn Musulumi ti kirun lasiko ọdún
Àkọlé àwòrán,
Awọn ara Ijebu n se ajọyọ ọdun ileya ni Eid Prayer Arena, Igbeba - Ijebu-Ode
Àkọlé àwòrán,
Àwọn ọmọ ọlọdun ń yẹra wo l'Osogbo
Àkọlé àwòrán,
Lọjọ ọdún yí àwọn mùsùlùmí yóò ki Irun rakaah méjì leyin tí Imam yoo pa eran tirẹ.
Àkọlé àwòrán,
Ọdun Ileya yii dun ni Ijẹbu, ẹsin ni ọmọde yii fi n jaye.
Àkọlé àwòrán,
Leyin ti Imam ba pa eran tan ni awon janmọ to ku le pa ti wọn náà
Àkọlé àwòrán,
Ní àwọn Aaye ìkìrun ati ọkunrin ati obirin ló peju
Àkọlé àwòrán,
Ọdun ba wa ni aye ati ni alaafia, o ye ka jo, ka si tun yọ pẹlu.
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ati oni ilu fi ilu se idaraya fun awọn eniyan lasiko ayeye ileya ti ọdun yii.
Àkọlé àwòrán,
Awọn agbagba ni ilu Ibadan naa o gbeyin nibi ọdun ileya ni yidi Agodi, ilu Ibadan.
Àkọlé àwòrán,
Ọ̀pọ awọn olutaja lasiko odun yii lo n pariwo ko sowo nita rara lọdun Ileya yii.
Àkọlé àwòrán,
Ẹ ri ẹgbẹ wa bi, o yẹ wa n ti wa
Oríṣun àwòrán,
@BashirAhmaad
Àkọlé àwòrán,
Eegun nla lo n kẹyin igbalẹ́, aarẹ Muhammadu Buhari naa du ẹran ọdun
Móríwú
01:13
Fídíò,
Mọ̀ nípa àwọn ewu méje tó rọ̀ mọ́ ṣíṣe ìdí ńlá, BBL, àti ìlànà tí wọ́n ń gbà ṣe é
, Duration 1,13
01:03
Fídíò,
Àwọn ọ̀dọ̀ ilẹ̀ Africa ni ìlera ọpọlọ wọn pé jù lọ láàgbáyé-Ìwádìí
, Duration 1,03
01:57
Fídíò,
DJ Cuppy ṣàlàyé ìdí tí inú rẹ̀ fi dùn pé Ààrẹ Tinubu ṣàbẹ̀wò sí ilẹ̀ UK
, Duration 1,57
04:18
Fídíò,
Ìlú kan rèé lábẹ́ ìjọba Ogun àmọ́ ilẹ̀ Benin ni wọn ti ń bímọ, pọn omi, ta ọjà pẹ̀lú ìnira ńlá
, Duration 4,18
04:54
Fídíò,
Agboolé Akọni: Ohun tó fa ìjà láàárín Afonja àti Aláàfin Aole àti bí Alimi ṣe dìtẹ̀gbàjọba lọ́wọ́ Afonja nítorí ẹ̀sìn
, Duration 4,54
01:27
Fídíò,
Ohun tó máa ń mú kí ọkùnrin máa rí àpẹrẹ pé òun lóyún nígbà tí ìyàwó rẹ̀ bá lóyún; COUVAD sydrome ni, ohun tó sì ń fàá rèé
, Duration 1,27
04:16
Fídíò,
Torí pé àwọn èèyàn ò rí ààrín èmi àti Allwell Ademola ni wọ́n fi ń sọ pé a ń fẹ́ra, àmọ́ Ọlọ́run yan án sínú ayé mi láti tọ́ mi sọ́nà – Rotimi Salami oṣere
, Duration 4,16
00:59
Fídíò,
Àwọn awakọ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tò ra epo pẹ̀lú bí owó epo ṣe ń lọ sókè
, Duration 0,59
03:03
Fídíò,
Wo tọkọtaya tó ń gba àwẹ̀ Lent àti Ramadan papọ̀
, Duration 3,03
01:44
Fídíò,
Wo àkóbá tó wà nínú àgbàdo, ẹ̀wà àti ata tí a lọ̀ ní ẹ̀rọ ìlọta fún ẹ̀dọ̀ àti kíndìnrín rẹ
, Duration 1,44
05:52
Fídíò,
Ohun táwọn oníṣẹ̀ṣe sọ fún àjọ INEC lórí ìdìbò àti pàtàkì ọdún Ọ̀ṣun Osogbo tí wọ́n fi yí ọjọ́ ìdìbò gómìnà padà
, Duration 5,52
Ìròyìn tó ṣe kókó
"Mo ra ‘Sim Card’ táwọn ajínigbé ti fi gbá owó ìtúsílẹ̀ N50m, pa ẹni tí wọn jí gbé, mo bá dèrò àtìmọ́lé"
wákàtí 5 sẹ́yìn
Kí ló fà á tí Funke Akindele kò fi dáhùn kíkí tí Toyin Abraham kí i lóde?
wákàtí 5 sẹ́yìn
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
wákàtí kan sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Mo ti bí ọmọ márùn-ún tẹ́lẹ̀ kí n tó bí ibẹ́rin báyìí, ìbejì ni scan sọ fún mi- Ìyá Ìbẹ́rin
23 Ẹrẹ̀nà 2026
Mo tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ẹ̀yin ọmọ Naijiria fún iná ọba tí kò sí lásìkò yìí- Adelabu
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Èmi ṣì ni alága NURTW- MC Oluomo
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ẹni tí kò bá dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027 rè é - Portable
25 Ẹrẹ̀nà 2026
'Biola Bayo, mo fà ẹ́ sí kóòtù Ọlọ́run'-Princess bú sígbe torí Baba Ijesa tí Biola Bayo gbé wá sóri ètò
25 Ẹrẹ̀nà 2026
NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Àwọn jàndùkú ya wọ ọ́fíìsì Amotekun l'Osun, jí ìbọn wọn gbé sálọ
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Àwọn agbésùnmọ̀mí tó jí ọmọ ìjọ ECWA mẹ́jọ gbé ní Kwara ń bèèrè bílíọ̀nù kan náírà fún ìtúsílẹ̀ wọn
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Àlàyé lórí ọ̀nà tuntun tí Amẹrika fẹ́ gbà láti fìyà jẹ orílẹ́èdè Iran
26 Ẹrẹ̀nà 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Kí ló fà á tí Funke Akindele kò fi dáhùn kíkí tí Toyin Abraham kí i lóde?
2
Àjọ̀dún Lisabi 2026 gbọ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀ lóòótọ́, àmọ́, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mẹ́yẹ bọ̀ lápò ni - Amosun
3
Agbèbọ́n tún ṣọṣẹ́ ní Plateau, pa ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́jọ́ Ìsinmi Ọ̀pẹ
4
Wo ohun tó mú àyájọ́ ọjọ́ ìsinmi 'Palm Sunday' yàtọ̀
5
Agbébọn tó kó òṣìṣẹ́ mẹ́ta lọ nílé ìwòsàn l'Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
6
Agbébọn 38 pàdé ikú lọ́wọ́ ológun Naijiria, wọ́n gba ìbọn AK-47 àti àdó olóró lọ́wọ́ wọn
7
Ìdí tí mi ò ṣe kí ń lo ọkọ mi ṣùgbọ́n tí mo máa ń lo ọmọ mi nínú fídíò àwàdà tí mò ń ṣe rèé - Kiekie
8
Yilwatda wọlé padà bíi Alága àpapọ̀ APC pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́
9
'Ìwà ọ̀daràn sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyan tó burú jùlọ': Ṣé ó yẹ káwọn orílẹ̀ èdè tó kó ilẹ̀ Africa san owó gbà mábinú?
10
Àwọn agbébọn kọlu àwọn to ń gbé òkú lọ itẹ́ ní Kwara, yìnbọn pa fijilanté méjì, jí ọ̀kadà àti ìbọn wọn lọ
Trending Now